diacritcs
stringlengths
1
36.7k
no_diacritcs
stringlengths
1
35.5k
parun)... Dájúdájú Musa wa bá
parun)... Dajudaju Musa wa ba
wọn pẹ̀lú ẹ̀rí tí ô dájú ṣùgbọn
won pelu eri ti o daju sugbon
wọn ṣe ìgbéraga lorií ilẹ̀, síbẹ̀síbẹ̀
won se igberaga lorii ile, sibesibe
wọn kò le mòríbọ lọwọ Wa.
won ko le moribo lowo Wa.
41. Nitorí náà òẹkọòọkan nínú wọn
41. Nitori naa oekoookan ninu won
la gbámú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀. Ò n bẹ
la gbamu nitori ese re. O n be
nínú wọn tí A rán ìjì lile sí, ô sìn
ninu won ti A ran iji lile si, o sin
bẹ nínú wọn tí A fi ìrúô òjijì
be ninu won ti A fi iruo ojiji
gbámú, o sì tún n bẹ nínú wọn tí
gbamu, o si tun n be ninu won ti
A jẹ kí ilẹ̀ gbémì; bákan náà ni A
A je ki ile gbemi; bakan naa ni A
tẹ àwọn kan rì sínú omi. Kì í ṣe
te awon kan ri sinu omi. Ki i se
pé Allah ṣe àbòsí fún wọn
pe Allah se abosi fun won
ṣùgbọn àwọn ni wỌn ṣàbòsí fún
sugbon awon ni wOn sabosi fun
ẹ̀mí ara Wọn.
emi ara Won.
42. Àpẹ̀júwe àwọn tò mú àwọn
42. Apejuwe awon to mu awon
Olùrànlẹwọ. míràn lẹhìn. Allah
Oluranlewo. miran lehin. Allah
dàbí àpẹ̀júwe alaáùtakùn tí ô kọlé
dabi apejuwe alaautakun ti o kole
fúnrarẹ̀, dájúdájú ilé tí O sì jẹ̀
funrare, dajudaju ile ti O si je
yẹpẹrẹ jùlọ ni ilé aláìtakùn, bí ô
yepere julo ni ile alaitakun, bi o
bá jẹ wí pé wọn mọ ni!
ba je wi pe won mo ni!
43... Dájúdáúdú. Allhh. mọ
43... Dajudaudu. Allhh. mo
ohunkQhun tí wọn n pẹ lẹhìn Rẹ̀;
ohunkQhun ti won n pe lehin Re;
Òun ni A lágbára, Ọlògbòn jùlọ.
Oun ni A lagbara, Ologbon julo.
Níbẹ̀ ni pẹpẹ wúrà wà fún sísun turari, ati àpótí majẹmu tí a fi wúrà bò yíká. Ninu àpótí yìí ni apẹ wúrà kékeré kan wà tí wọ́n fi mana sí ninu, ati ọ̀pá Aaroni tí ó rúwé nígbà kan rí, ati àwọn wàláà òkúta tí a kọ òfin mẹ́wàá sí. Mànàmáná ati ìró ààrá ń jáde láti ara ìtẹ́ tí ó wà láàrin. Ògùṣọ̀ meje tí iná wọn ń jó wà níwájú ìtẹ́ náà. Àwọn yìí ni Ẹ̀mí Ọlọrun meje. Ògiri kan wà níwájú àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ náà, ó ga ní igbọnwọ kan ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji. Ati òòró ati ìbú àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ náà jẹ́ igbọnwọ mẹfa mẹfa (mita 3). kí ohun ìrúbọ náà baà lè jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà, ó níláti jẹ́ akọ, tí kò ní àbùkù, ó lè jẹ́ akọ mààlúù, tabi àgbò, tabi òbúkọ. Nígbà tí àwọn tí ó fi ẹ̀sùn kàn án dìde láti sọ̀rọ̀, wọn kò mẹ́nuba irú àwọn ọ̀ràn tí mo rò pé wọn yóo sọ. Ní tèmi, bí a bá gbé mi sókè kúrò láyé, n óo fa gbogbo eniyan sọ́dọ̀ mi.” Ìlú ìdàrúdàpọ̀ ti wó palẹ̀, ó ti dòfo,gbogbo ìlẹ̀kùn ilé ti tì, kò sì sí ẹni tí ó lè wọlé.Ohun ìdọ̀tí kan kò ní wọ inú rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó bá ń ṣe ohun ẹ̀gbin tabi èké kò ní wọ ibẹ̀. Àwọn tí a ti kọ orúkọ wọn sinu ìwé ìyè Ọ̀dọ́ Aguntan nìkan ni yóo wọ ibẹ̀. Ṣugbọn àwọn kan ninu wọn ń sọ pé, “Agbára Beelisebulu, olórí àwọn ẹ̀mí èṣù, ni ó fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.” ẹ̀yin tí ẹ̀ ń wí fún igi pé igi ni baba yín,tí ẹ sì ń sọ fún òkúta pé òkúta ni ó bi yín;nítorí pé dípò kí ẹ kọjú sí ọ̀dọ̀ mi,ẹ̀yìn ni ẹ kọ sí mi.Ṣugbọn nígbà tí ìṣòro dé ba yín,ẹ bẹ̀rẹ̀ sí kígbe pè mí pé kí n dìde, kí n gbà yín là.Kí ni ẹ ní lọ́wọ́? Fún mi ní ìṣù burẹdi marun-un tabi ohunkohun tí o bá ní.”Ṣebí ẹni tí ó dá mi ninu oyún,òun kan náà ló dá iranṣẹ mi?Òun ló mọ wá kí wọn tó bí wa.nípa ohun tí ẹ bá ṣe àṣìṣe rẹ̀, àyàfi
Nibe ni pepe wura wa fun sisun turari, ati apoti majemu ti a fi wura bo yika. Ninu apoti yii ni ape wura kekere kan wa ti won fi mana si ninu, ati opa Aaroni ti o ruwe nigba kan ri, ati awon walaa okuta ti a ko ofin mewaa si. Manamana ati iro aara n jade lati ara ite ti o wa laarin. Oguso meje ti ina won n jo wa niwaju ite naa. Awon yii ni Emi Olorun meje. Ogiri kan wa niwaju awon yara egbe naa, o ga ni igbonwo kan ni egbe kinni keji. Ati ooro ati ibu awon yara egbe naa je igbonwo mefa mefa (mita 3). ki ohun irubo naa baa le je itewogba, o nilati je ako, ti ko ni abuku, o le je ako maaluu, tabi agbo, tabi obuko. Nigba ti awon ti o fi esun kan an dide lati soro, won ko menuba iru awon oran ti mo ro pe won yoo so. Ni temi, bi a ba gbe mi soke kuro laye, n oo fa gbogbo eniyan sodo mi.” Ilu idarudapo ti wo pale, o ti dofo,gbogbo ilekun ile ti ti, ko si si eni ti o le wole.Ohun idoti kan ko ni wo inu re. Bee ni eni ti o ba n se ohun egbin tabi eke ko ni wo ibe. Awon ti a ti ko oruko won sinu iwe iye Odo Aguntan nikan ni yoo wo ibe. Sugbon awon kan ninu won n so pe, “Agbara Beelisebulu, olori awon emi esu, ni o fi n le awon emi esu jade.” eyin ti e n wi fun igi pe igi ni baba yin,ti e si n so fun okuta pe okuta ni o bi yin;nitori pe dipo ki e koju si odo mi,eyin ni e ko si mi.Sugbon nigba ti isoro de ba yin,e bere si kigbe pe mi pe ki n dide, ki n gba yin la.Ki ni e ni lowo? Fun mi ni isu buredi marun-un tabi ohunkohun ti o ba ni.”Sebi eni ti o da mi ninu oyun,oun kan naa lo da iranse mi?Oun lo mo wa ki won to bi wa.nipa ohun ti e ba se asise re, ayafi
lrí ohun tí ọkàn yín bá ti
lri ohun ti okan yin ba ti
mọ-Ọn-mọ. ṣe.. Allah sì jẹ
mo-On-mo. se.. Allah si je
Alaàforíjìn, Aláàánú jùlọ.
Alaaforijin, Alaaanu julo.
7. Ànábì sunmọ àwọn onígbàgbọ
7. Anabi sunmo awon onigbagbo
òdodo ju àwọn fúnra wọn. lọ.
ododo ju awon funra won. lo.
Àwọn ìyàwò. rẹ̀ sì JẸ iya Wọn,
Awon iyawo. re si JE iya Won,
àwọn ìbátan nínú ẹ̀jẹ̀ sì súnmọ
awon ibatan ninu eje si sunmo
ara wọn nínú àkọrsílẹ̀ ti Allah ju
ara won ninu akorsile ti Allah ju
àwọn onígbàgbọ òdodo mìíràn,
awon onigbagbo ododo miiran,
àti àwọn tô bá Ànábì jáde ní
ati awon to ba Anabi jade ni
Mákà, àyàfi kí ẹ máa ṣe rere sí
Maka, ayafi ki e maa se rere si
àwọn ọrẹ̀ yín. Éyí Jjẹ ohun tí a kọ
awon ore yin. Eyi Jje ohun ti a ko
sílẹ̀ nínú Ìwé náà.
sile ninu Iwe naa.
8. Ṣe ìrántí ìgbà tí A bá àwọn
8. Se iranti igba ti A ba awon
Anabi dá májẹ̀mú, àti ìwọ náà,
Anabi da majemu, ati iwo naa,
àti Nuha, àti Ibrahim, àti Músá,
ati Nuha, ati Ibrahim, ati Musa,
pẹ̀lú Isa ọmọ Maryamọ. A sì bá
pelu Isa omo Maryamo. A si ba
gbogbo wọn dá maàjẹ̀mú tí ô fẹsẹ̀
gbogbo won da maajemu ti o fese
rinjẹ̀.
rinje.
9, Kí Òun baà lẹ̀ bi àwọn
9, Ki Oun baa le bi awon
olododo léẹ̀rẹò nípa òdodo wọn.
olododo leereo nipa ododo won.
Oún sì ti pẹ̀s ìyà olôrò sílẹ̀ fún
Oun si ti pes iya oloro sile fun
àwọn aláìgbàgbọ.
awon alaigbagbo.
ÌDÁ 2
IDA 2
10. Ẹyin onígbàgbọ òdodo, ẹ
10. Eyin onigbagbo ododo, e
rántí ojú rere Allah lòrí yín,
ranti oju rere Allah lori yin,
nígbà tí àwọn ọmọ ogun kan kọlù
nigba ti awon omo ogun kan kolu
yin, tí Àwa sì rán atẹgùn sí wọn
yin, ti Awa si ran ategun si won
àti àwọn ọmọ ogun kan tí ẹ̀yin kò
ati awon omo ogun kan ti eyin ko
ri. Allah sì n rí ohun tí ẹ n ṣe.
ri. Allah si n ri ohun ti e n se.
11. Nígbà tí wọn kọlù yín láti
11. Nigba ti won kolu yin lati
òkò yín, àti láti ìsàlẹ̀ yín, àti nígbà
oko yin, ati lati isale yin, ati nigba
Gun orí òkè gíga lọ, ìwọ Sioni,kí o máa kéde ìyìn rere.Gbé ohùn rẹ sókè pẹlu agbára Jerusalẹmu,ìwọ tí ò ń kéde ìyìn rereké sókè má ṣe bẹ̀rù;sọ fún àwọn ìlú Juda pé,“Ẹ wo Ọlọrun yín.”Kuṣi ni baba Nimrodu, Nimrodu yìí ni ẹni kinni tí wọ́n mọ̀ ní akọni láyé. Mo bẹ̀ yín, ẹ dúró bẹ́ẹ̀,kí ẹ má baà ṣẹ̀.Ẹ dúró bẹ́ẹ̀, nítorí n kò lẹ́bi.Abrahamu fẹ́ aya mìíràn, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ketura. “Ẹ gbọdọ̀ ṣàkíyèsí òfin mi, kí ẹ sì máa pa wọ́n mọ́. Èmi ni OLUWA. Judasi bá da owó náà sílẹ̀ ninu Tẹmpili, ó jáde, ó bá lọ pokùnso.Nítorí oore-ọ̀fẹ́ ní a fi gbà yín là nípa ìgbàgbọ́. Èyí kì í ṣe nípa agbára ẹ̀yin fúnrayín: ẹ̀bùn Ọlọ́run ni: Malikija ọmọ Rekabu, aláṣẹ agbègbè Beti Hakikeremu, ṣe àtúnṣe Ẹnubodè Ààtàn, ó tún un kọ́, ó so àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀ ó sì ṣe àwọn ìdábùú rẹ̀.Wọ́n sọ fún ìjọ eniyan Israẹli pé, “Ilẹ̀ tí a lọ wò náà jẹ́ ilẹ̀ tí ó dára lọpọlọpọ. Ọmọ-Eniyan yóo rán àwọn angẹli rẹ̀, wọn yóo kó gbogbo àwọn amúni-ṣìnà ati àwọn arúfin kúrò ninu ìjọba rẹ̀. Kò sí ẹni tí ó ní ìfẹ́ tí ó ju èyí lọ, pé ẹnìkan kú nítorí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀. If a child learns the trick of crying, the mother learns the trick of consoling him or her.
Gun ori oke giga lo, iwo Sioni,ki o maa kede iyin rere.Gbe ohun re soke pelu agbara Jerusalemu,iwo ti o n kede iyin rereke soke ma se beru;so fun awon ilu Juda pe,“E wo Olorun yin.”Kusi ni baba Nimrodu, Nimrodu yii ni eni kinni ti won mo ni akoni laye. Mo be yin, e duro bee,ki e ma baa se.E duro bee, nitori n ko lebi.Abrahamu fe aya miiran, ti oruko re n je Ketura. “E gbodo sakiyesi ofin mi, ki e si maa pa won mo. Emi ni OLUWA. Judasi ba da owo naa sile ninu Tempili, o jade, o ba lo pokunso.Nitori oore-ofe ni a fi gba yin la nipa igbagbo. Eyi ki i se nipa agbara eyin funrayin: ebun Olorun ni: Malikija omo Rekabu, alase agbegbe Beti Hakikeremu, se atunse Enubode Aatan, o tun un ko, o so awon ilekun re o si se awon idabuu re.Won so fun ijo eniyan Israeli pe, “Ile ti a lo wo naa je ile ti o dara lopolopo. Omo-Eniyan yoo ran awon angeli re, won yoo ko gbogbo awon amuni-sina ati awon arufin kuro ninu ijoba re. Ko si eni ti o ni ife ti o ju eyi lo, pe enikan ku nitori awon ore re. If a child learns the trick of crying, the mother learns the trick of consoling him or her.
Àwọn ìràwọ̀ yóo máa já bọ́ láti ojú ọ̀run, a óo wá mi gbogbo àwọn ogun ọ̀run. OLUWA àwọn ọmọ ogun, ìwọ tíí dán olódodo wò,ìwọ tí o mọ ọkàn ati èrò eniyan.Gbẹ̀san lára wọn kí n fojú rí i,nítorí ìwọ ni mo fi ọ̀rọ̀ mi lé lọ́wọ́.Ṣugbọn n óo rúbọ sí ọ pẹlu ohùn ọpẹ́,n óo sì san ẹ̀jẹ́ mi.Ti OLUWA ni ìgbàlà!”Jesu sọ fún un pé, “Ìdí rẹ̀ tí o fi ń pè mí ní ẹni rere? Kò sí ẹni rere kan àfi Ọlọrun nìkan ṣoṣo. Bí o kò gbọ́ Ègùn, o kò gbọ́ wọ̀yọ̀-wọ̀yọ̀?
Awon irawo yoo maa ja bo lati oju orun, a oo wa mi gbogbo awon ogun orun. OLUWA awon omo ogun, iwo tii dan olododo wo,iwo ti o mo okan ati ero eniyan.Gbesan lara won ki n foju ri i,nitori iwo ni mo fi oro mi le lowo.Sugbon n oo rubo si o pelu ohun ope,n oo si san eje mi.Ti OLUWA ni igbala!”Jesu so fun un pe, “Idi re ti o fi n pe mi ni eni rere? Ko si eni rere kan afi Olorun nikan soso. Bi o ko gbo Egun, o ko gbo woyo-woyo?
Èmi ni OLUWA Ọlọrun rẹ, tí ó mú ọ jáde wá láti ilẹ̀ Ijipti, láti fi ilẹ̀ Kenaani fún ọ ati láti jẹ́ Ọlọrun rẹ.Wọ́n dá a lóhùn pé, “Rárá, àwa óo dì ọ́, a óo sì gbé ọ lé wọn lọ́wọ́ ni, a kò ní pa ọ́ rárá.” Wọ́n bá mú okùn titun meji, wọ́n fi dì í, wọ́n sì gbé e jáde láti inú ihò àpáta náà.Lójijì, Absalomu já sí ààrin àwọn ọmọ ogun Dafidi. Ìbaaka ni Absalomu gùn. Ìbaaka yìí gba abẹ́ ẹ̀ka igi Oaku ńlá kan, ẹ̀ka igi yìí sì dí tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi kọ́ Absalomu ní irun orí, Ìbaaka yọ lọ lábẹ́ rẹ̀, Absalomu sì ń rọ̀ dirodiro nítorí pé ẹsẹ̀ rẹ̀ kò tólẹ̀. Nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun, dìde, lọ sí ibùjókòó rẹ, ìwọ ati àpótí ẹ̀rí agbára rẹ. Gbé ìgbàlà rẹ wọ àwọn alufaa rẹ bí ẹ̀wù, kí o sì jẹ́ kí àwọn eniyan mímọ́ rẹ yọ̀ ninu ire rẹ. Olólùfẹ́ mi, mo fi ọ́ wé akọ ẹṣin tí ń fa kẹ̀kẹ́ ogun Farao.Jobu bá dìde, ó fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn; ó fá orí rẹ̀, ó dojúbolẹ̀, ó sì sin OLUWA. Kí ẹ gba ilẹ̀ náà kí ẹ sì máa gbé inú rẹ̀, nítorí pé mo ti fun yín gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ ìní yín. Nítorí pé ọjọ́ kan péré ninu àgbàlá rẹ,ṣe anfaani ju ẹgbẹrun ọjọ́ níbòmíràn lọ.Ó wù mí kí n jẹ́ aṣọ́nà ninu ilé Ọlọrun miju pé kí n máa gbé inú àgọ́ àwọn eniyan burúkú.“Ṣé o lè fokùn so ìràwọ̀ Pileiadesi,tabi kí o tú okùn ìràwọ̀ Orioni?Paulu dáhùn pé, “Ará, n kò mọ̀ pé Olórí Alufaa ni. Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ sọ̀rọ̀ burúkú sí aláṣẹ àwọn eniyan rẹ.’ ” OLUWA, o óo gbọ́ ohùn mi ní òwúrọ̀,ní òwúrọ̀ ni n óo máa sọ ẹ̀dùn ọkàn mi fún ọ;èmi óo sì máa ṣọ́nà.N óo mú kí wọn máa pa ọmọ wọn ọkunrin ati obinrin jẹ. Olukuluku yóo máa pa aládùúgbò rẹ̀ jẹ nítorí ìdààmú tí àwọn ọ̀tá wọn, ati àwọn tí ń wá ẹ̀mí wọn yóo kó bá wọn, nígbà tí ogun bá dótì wọ́n.”Láti Alimoni Dibilataimu wọ́n lọ sí Òkè Abarimu níwájú Nebo. Ìpín ti Nafutali yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ti Aṣeri, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn. “Ta ló lànà fún ọ̀wààrà òjò,ati fún ààrá,Wò ó, eniyan burúkú lóyún ibi, ó lóyún ìkà, ó sì bí èké.Ọ̀run ati ayé yóo kọjá lọ, ṣugbọn ọ̀rọ̀ mi kò ní kọjá lọ.If you do not understand Ègùn, do you not recognize signs that someone is speaking?
Emi ni OLUWA Olorun re, ti o mu o jade wa lati ile Ijipti, lati fi ile Kenaani fun o ati lati je Olorun re.Won da a lohun pe, “Rara, awa oo di o, a oo si gbe o le won lowo ni, a ko ni pa o rara.” Won ba mu okun titun meji, won fi di i, won si gbe e jade lati inu iho apata naa.Lojiji, Absalomu ja si aarin awon omo ogun Dafidi. Ibaaka ni Absalomu gun. Ibaaka yii gba abe eka igi Oaku nla kan, eka igi yii si di tobee ti o fi ko Absalomu ni irun ori, Ibaaka yo lo labe re, Absalomu si n ro dirodiro nitori pe ese re ko tole. Nisinsinyii, OLUWA Olorun, dide, lo si ibujokoo re, iwo ati apoti eri agbara re. Gbe igbala re wo awon alufaa re bi ewu, ki o si je ki awon eniyan mimo re yo ninu ire re. Ololufe mi, mo fi o we ako esin ti n fa keke ogun Farao.Jobu ba dide, o fa aso re ya lati fi ibanuje re han; o fa ori re, o dojubole, o si sin OLUWA. Ki e gba ile naa ki e si maa gbe inu re, nitori pe mo ti fun yin gege bi ile ini yin. Nitori pe ojo kan pere ninu agbala re,se anfaani ju egberun ojo nibomiran lo.O wu mi ki n je asona ninu ile Olorun miju pe ki n maa gbe inu ago awon eniyan buruku.“Se o le fokun so irawo Pileiadesi,tabi ki o tu okun irawo Orioni?Paulu dahun pe, “Ara, n ko mo pe Olori Alufaa ni. Nitori o wa ni akosile pe, ‘Iwo ko gbodo soro buruku si alase awon eniyan re.’ ” OLUWA, o oo gbo ohun mi ni owuro,ni owuro ni n oo maa so edun okan mi fun o;emi oo si maa sona.N oo mu ki won maa pa omo won okunrin ati obinrin je. Olukuluku yoo maa pa aladuugbo re je nitori idaamu ti awon ota won, ati awon ti n wa emi won yoo ko ba won, nigba ti ogun ba doti won.”Lati Alimoni Dibilataimu won lo si Oke Abarimu niwaju Nebo. Ipin ti Nafutali yoo wa legbee ti Aseri, lati ila oorun titi de iwo oorun. “Ta lo lana fun owaara ojo,ati fun aara,Wo o, eniyan buruku loyun ibi, o loyun ika, o si bi eke.Orun ati aye yoo koja lo, sugbon oro mi ko ni koja lo.If you do not understand Egun, do you not recognize signs that someone is speaking?
“Gbà wá ní ìmọ̀ràn,máa ṣe ẹ̀tọ́ fún wa.Fi òjìji rẹ dáàbò bò wá,kí ara lè tù wá lọ́sàn-án gangan,bí ẹni pé alẹ́ ni.Dáàbò bo àwọn tí a lé jáde;má tú àṣírí ẹni tí ń sálọ.Ọlọrun bá a sọ̀rọ̀ lójú ìran lóru, ó pè é, ó ní, “Jakọbu, Jakọbu.”Ó dáhùn, ó ní, “Èmi nìyí.”Ó kó ọpọlọpọ irin jọ, tí wọn óo fi rọ ìṣó, tí wọn yóo fi kan àwọn ìlẹ̀kùn ati ìdè, ó kó idẹ jọ lọpọlọpọ pẹlu, ju ohun tí ẹnikẹ́ni lè wọ̀n lọ, Talaka kan wà tí ó ń jẹ́ Lasaru, tíí máa ń jókòó lẹ́nu ọ̀nà ilé ọlọ́rọ̀ yìí. Gbogbo ara Lasaru jẹ́ kìkì egbò. Bí ọmọ́ bá jágbọ́n-ọn kíké, ìyá-a rẹ̀ a jágbọ́n-ọn rírẹ̀ ẹ́.
“Gba wa ni imoran,maa se eto fun wa.Fi ojiji re daabo bo wa,ki ara le tu wa losan-an gangan,bi eni pe ale ni.Daabo bo awon ti a le jade;ma tu asiri eni ti n salo.Olorun ba a soro loju iran loru, o pe e, o ni, “Jakobu, Jakobu.”O dahun, o ni, “Emi niyi.”O ko opolopo irin jo, ti won oo fi ro iso, ti won yoo fi kan awon ilekun ati ide, o ko ide jo lopolopo pelu, ju ohun ti enikeni le won lo, Talaka kan wa ti o n je Lasaru, tii maa n jokoo lenu ona ile oloro yii. Gbogbo ara Lasaru je kiki egbo. Bi omo ba jagbon-on kike, iya-a re a jagbon-on rire e.
Yóo ṣe ìdájọ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè; yóo sì bá ọpọlọpọ eniyan wí.Wọn yóo fi idà wọn rọ ọkọ́,wọn yóo sì fi ọ̀kọ̀ wọn rọ dòjé.Àwọn orílẹ̀-èdè kò ní yọ idà sí ara wọn mọ́,wọn kò sì ní kọ́ ogun jíjà mọ́.Ó mọ odi yí mi ká,ó sì fi ẹ̀wọ̀n wúwo dè mí,kí n má baà lè sálọ.Ìṣòro kinni kọjá; ṣugbọn ó tún ku meji lẹ́yìn èyí.“Bí ẹ bá gba irú ẹran bẹ́ẹ̀ lọ́wọ́ àlejò, ẹ kò gbọdọ̀ fi rú ẹbọ ohun jíjẹ sí èmi Ọlọrun yín. Níwọ̀n ìgbà tí àbùkù bá ti wà lára wọn, OLUWA kò ní tẹ́wọ́gba irú wọn lọ́wọ́ yín, nítorí àbùkù náà.”Fẹstu wá sọ pé, “Agiripa aláyélúwà ati gbogbo ẹ̀yin eniyan tí ẹ bá wa péjọ níbí. Ọkunrin tí ẹ̀ ń wò yìí ni gbogbo àwọn Juu ní Jerusalẹmu ati níbí ń yan eniyan wá rí mi nípa rẹ̀, tí wọn ń kígbe pé kò yẹ kí ó tún wà láàyè mọ́. Gbogbo àwọn ará Juda tí wọ́n wà ní ìgbèkùn ní Babiloni yóo máa fi ọ̀rọ̀ wọn ṣépè fún eniyan pé: ‘OLUWA yóo ṣe ọ́ bíi Sedekaya ati Ahabu tí ọba Babiloni sun níná,’ Gbogbo yín, ẹ máa ṣọ́nà, kí ẹ tún máa gbadura, kí ẹ má baà bọ́ sinu ìdánwò. Ẹ̀mí fẹ́ ṣe é, ṣugbọn ara kò lágbára.”Àbí ọmọ gbẹ́nà-gbẹ́nà yẹn kọ́ ni? Tí orúkọ ìyá rẹ̀ ń jẹ́ Maria, tí àwọn arakunrin rẹ̀ ń jẹ́ Jakọbu ati Josẹfu ati Simoni ati Judasi? Nígbà tí ọ̀pọ̀ eniyan péjọ yí i ká, ó bẹ̀rẹ̀ sí wí pé, “Ìran burúkú ni ìran yìí; ó ń wá àmì. Kò sí àmì kan tí a óo fún un àfi àmì Jona. Àwọn eniyan kẹ́gàn rẹ̀,wọ́n sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀;ẹni tí inú rẹ̀ bàjẹ́ tí ó sì mọ ìkáàánú ni.Ó dàbí ẹni tí àwọn eniyan ń wò ní àwòpajúdà.A kẹ́gàn rẹ̀, a kò sì kà á kún.Àwọn ni wọn óo kọ́ ọ,tí wọn óo bá ọ sọ̀rọ̀,tí wọn óo sì fún ọ ní ìmọ̀ràn ninu òye wọn. “Ẹ mọ oríṣìíríṣìí ọ̀nà tí eniyan fi í wá olólùfẹ́ kiri,tóbẹ́ẹ̀ tí ẹ ti fi ìrìnkurìn yínkọ́ àwọn obinrin oníwà burúkú.Ju ohun gbogbo lọ, ẹ ní ìfẹ́ tí ó jinlẹ̀ sí ara yín, nítorí ìfẹ́ bo ọpọlọpọ ẹ̀ṣẹ̀ mọ́lẹ̀. Àwọn eniyan Juda bá dáhùn pé, “Ìdí tí a fi ṣe bẹ́ẹ̀ ni pé, ọ̀kan náà ni àwa ati ọba. Kí ló dé tí èyí fi níláti bà yín ninu jẹ́? Kì í ṣá ṣe pé òun ni ó ń bọ́ wa, a kò sì gba nǹkankan lọ́wọ́ rẹ̀.”tí OLUWA ti ran àwọn ọmọ Israẹli lọ́wọ́ láti gbà jẹ́ ilẹ̀ tí ó dára fún ẹran ọ̀sìn, àwa iranṣẹ yín sì ní ẹran ọ̀sìn pupọ. A kò fi ohun ìkọsẹ̀ kankan siwaju ẹnikẹ́ni, kí àwọn eniyan má baà rí wí sí iṣẹ́ wa. Àwọn agbéraga ti dẹ tàkúté sílẹ̀ dè mí,wọ́n dẹ àwọ̀n sílẹ̀ fún mi;wọ́n sì dẹ okùn sílẹ̀ fún mi lẹ́bàá ọ̀nà.Nítorí kì í ṣe nítorí pé Abrahamu pa Òfin mọ́ ni Ọlọrun fi ṣe ìlérí fún òun ati ìran rẹ̀ pé yóo jogún ayé; nítorí ó gba Ọlọrun gbọ́ ni, Ọlọrun sì kà á sí ẹni rere. Ààlà ilẹ̀ tí wọ́n pín fún àwọn ọmọ Josẹfu bẹ̀rẹ̀ láti odò Jọdani lẹ́bàá Jẹriko, ní apá ìlà oòrùn àwọn odò Jẹriko, ó lọ títí dé apá aṣálẹ̀. Ó tún bẹ̀rẹ̀ láti Jẹriko lọ sí apá àwọn ìlú tí ó wà ní orí òkè, títí dé Bẹtẹli. Ó tún kọ́ àwọn ilé ìṣọ́ sinu aṣálẹ̀, ó gbẹ́ ọpọlọpọ kànga, nítorí pé ó ní ọpọlọpọ agbo ẹran ọ̀sìn ní àwọn ẹsẹ̀ òkè ati ní pẹ̀tẹ́lẹ̀. Ó ní àwọn òṣìṣẹ́ tí wọn ń dá oko fún un ati àwọn tí wọn ń ṣiṣẹ́ ninu àjàrà, lórí òkè ati lórí àwọn ilẹ̀ ọlọ́ràá, nítorí ó fẹ́ràn iṣẹ́ àgbẹ̀.Ọba Ijipti óo máa gbéraga nítorí ìṣẹ́gun rẹ̀ lórí ọpọlọpọ ogun yìí, yóo sì pa ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ ogun, ṣugbọn kò ní borí.Ọlọrun, tí mò ń fọkàn sìn bí mo ti ń waasu ìyìn rere Ọmọ rẹ̀, ni ẹlẹ́rìí mi pé mò ń ranti yín láì sinmi. tí ẹ bá rí arẹwà obinrin kan láàrin àwọn ẹrú náà tí ó wù yín láti fi ṣe aya fún ara yín. Gbogbo àwọn eniyan kún fún ayọ̀, gbogbo ìlú sì ní alaafia lẹ́yìn tí wọ́n ti fi idà pa Atalaya ní ààfin.Já a sí wẹ́wẹ́, kí o sì da òróró lé e lórí, ẹbọ ohun jíjẹ ni.Solomoni bá yọ Abiatari kúrò ninu iṣẹ́ alufaa OLUWA tí ó ń ṣe, ó sì jẹ́ kí ọ̀rọ̀ tí OLUWA sọ ní Ṣilo ṣẹ, nípa Eli alufaa ati arọmọdọmọ rẹ̀. N óo fi ẹ̀mí mi si yín ninu, n óo mú kí ẹ máa rìn ní ìlànà mi, kí ẹ sì máa fi tọkàntọkàn pa òfin mi mọ́. Ẹ̀hìn ológbò kì í balẹ̀.
Yoo se idajo laarin awon orile-ede; yoo si ba opolopo eniyan wi.Won yoo fi ida won ro oko,won yoo si fi oko won ro doje.Awon orile-ede ko ni yo ida si ara won mo,won ko si ni ko ogun jija mo.O mo odi yi mi ka,o si fi ewon wuwo de mi,ki n ma baa le salo.Isoro kinni koja; sugbon o tun ku meji leyin eyi.“Bi e ba gba iru eran bee lowo alejo, e ko gbodo fi ru ebo ohun jije si emi Olorun yin. Niwon igba ti abuku ba ti wa lara won, OLUWA ko ni tewogba iru won lowo yin, nitori abuku naa.”Festu wa so pe, “Agiripa alayeluwa ati gbogbo eyin eniyan ti e ba wa pejo nibi. Okunrin ti e n wo yii ni gbogbo awon Juu ni Jerusalemu ati nibi n yan eniyan wa ri mi nipa re, ti won n kigbe pe ko ye ki o tun wa laaye mo. Gbogbo awon ara Juda ti won wa ni igbekun ni Babiloni yoo maa fi oro won sepe fun eniyan pe: ‘OLUWA yoo se o bii Sedekaya ati Ahabu ti oba Babiloni sun nina,’ Gbogbo yin, e maa sona, ki e tun maa gbadura, ki e ma baa bo sinu idanwo. Emi fe se e, sugbon ara ko lagbara.”Abi omo gbena-gbena yen ko ni? Ti oruko iya re n je Maria, ti awon arakunrin re n je Jakobu ati Josefu ati Simoni ati Judasi? Nigba ti opo eniyan pejo yi i ka, o bere si wi pe, “Iran buruku ni iran yii; o n wa ami. Ko si ami kan ti a oo fun un afi ami Jona. Awon eniyan kegan re,won si ko o sile;eni ti inu re baje ti o si mo ikaaanu ni.O dabi eni ti awon eniyan n wo ni awopajuda.A kegan re, a ko si ka a kun.Awon ni won oo ko o,ti won oo ba o soro,ti won oo si fun o ni imoran ninu oye won. “E mo orisiirisii ona ti eniyan fi i wa ololufe kiri,tobee ti e ti fi irinkurin yinko awon obinrin oniwa buruku.Ju ohun gbogbo lo, e ni ife ti o jinle si ara yin, nitori ife bo opolopo ese mole. Awon eniyan Juda ba dahun pe, “Idi ti a fi se bee ni pe, okan naa ni awa ati oba. Ki lo de ti eyi fi nilati ba yin ninu je? Ki i sa se pe oun ni o n bo wa, a ko si gba nnkankan lowo re.”ti OLUWA ti ran awon omo Israeli lowo lati gba je ile ti o dara fun eran osin, awa iranse yin si ni eran osin pupo. A ko fi ohun ikose kankan siwaju enikeni, ki awon eniyan ma baa ri wi si ise wa. Awon agberaga ti de takute sile de mi,won de awon sile fun mi;won si de okun sile fun mi lebaa ona.Nitori ki i se nitori pe Abrahamu pa Ofin mo ni Olorun fi se ileri fun oun ati iran re pe yoo jogun aye; nitori o gba Olorun gbo ni, Olorun si ka a si eni rere. Aala ile ti won pin fun awon omo Josefu bere lati odo Jodani lebaa Jeriko, ni apa ila oorun awon odo Jeriko, o lo titi de apa asale. O tun bere lati Jeriko lo si apa awon ilu ti o wa ni ori oke, titi de Beteli. O tun ko awon ile iso sinu asale, o gbe opolopo kanga, nitori pe o ni opolopo agbo eran osin ni awon ese oke ati ni petele. O ni awon osise ti won n da oko fun un ati awon ti won n sise ninu ajara, lori oke ati lori awon ile oloraa, nitori o feran ise agbe.Oba Ijipti oo maa gberaga nitori isegun re lori opolopo ogun yii, yoo si pa ogunlogo awon omo ogun, sugbon ko ni bori.Olorun, ti mo n fokan sin bi mo ti n waasu iyin rere Omo re, ni elerii mi pe mo n ranti yin lai sinmi. ti e ba ri arewa obinrin kan laarin awon eru naa ti o wu yin lati fi se aya fun ara yin. Gbogbo awon eniyan kun fun ayo, gbogbo ilu si ni alaafia leyin ti won ti fi ida pa Atalaya ni aafin.Ja a si wewe, ki o si da ororo le e lori, ebo ohun jije ni.Solomoni ba yo Abiatari kuro ninu ise alufaa OLUWA ti o n se, o si je ki oro ti OLUWA so ni Silo se, nipa Eli alufaa ati aromodomo re. N oo fi emi mi si yin ninu, n oo mu ki e maa rin ni ilana mi, ki e si maa fi tokantokan pa ofin mi mo. Ehin ologbo ki i bale.
Gbẹ́ran-gbẹ́ran ò gbé ẹkùn.
Gberan-gberan o gbe ekun.
Wò ó! Baba mi, wo etí aṣọ rẹ tí mo mú lọ́wọ́ yìí, ǹ bá pa ọ́ bí mo bá fẹ́, ṣugbọn kàkà bẹ́ẹ̀, mo gé etí aṣọ rẹ. Ó yẹ kí èyí fihàn ọ́ pé n kò ní ìfẹ́ láti ṣọ̀tẹ̀ sí ọ, tabi láti pa ọ́. Ṣugbọn ìwọ ń lé mi kiri láti pa mí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kò ṣe ọ́ níbi. Mo kórìíra àwọn tí ń bọ oriṣa lásánlàsàn,ṣugbọn OLUWA ni èmi gbẹ́kẹ̀lé.Ó ń gbé ìlú tí ó ti di ahoro,ninu àwọn ilé tí eniyan kò gbọdọ̀ gbé,àwọn ilé tí yóo pada di òkítì àlàpà.Gbogbo àwọn olùṣọ́nà tí wọ́n yàn láti máa ṣọ́ ẹnu ọ̀nà àbáwọlé jẹ́ igba ó lé mejila (212). A kọ orúkọ wọn sinu ìwé gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn, ní agbègbè wọn. Dafidi ati Samuẹli aríran, ni wọ́n fi wọ́n sí ipò pataki náà. Gbọ́ tiwa, Ọlọrun mi, ṣíjú wò wá, bí àwa ati ìlú tí à ń pe orúkọ rẹ mọ́, ti wà ninu ìsọdahoro. Kì í ṣe nítorí òdodo wa ni a ṣe ń gbadura sí ọ, ṣugbọn nítorí pé aláàánú ni ọ́. Ṣugbọn Isaaki dáhùn pé, “Àbúrò rẹ ti wá pẹlu ẹ̀tàn, ó sì ti gba ìre rẹ lọ.”Ọ̀gá rẹ̀ bá pè é, ó sọ fún un pé, ‘Irú ìròyìn wo ni mò ń gbọ́ nípa rẹ yìí? Ṣírò iṣẹ́ rẹ bí ọmọ-ọ̀dọ̀, nítorí n óo dá ọ dúró lẹ́nu iṣẹ́.’ Jakọbu nífẹ̀ẹ́ Rakẹli, nítorí náà, ó sọ fún Labani pé, “N óo sìn ọ́ ní ọdún meje nítorí Rakẹli, ọmọ rẹ kékeré.”Àbí kì í ṣe láti ẹnu Ọ̀gá Ògoni rere ati burúkú ti ń jáde?Intemperate dandyism lands a youth in a creditor's farm as a pawn.
Wo o! Baba mi, wo eti aso re ti mo mu lowo yii, n ba pa o bi mo ba fe, sugbon kaka bee, mo ge eti aso re. O ye ki eyi fihan o pe n ko ni ife lati sote si o, tabi lati pa o. Sugbon iwo n le mi kiri lati pa mi, bi o tile je pe n ko se o nibi. Mo koriira awon ti n bo orisa lasanlasan,sugbon OLUWA ni emi gbekele.O n gbe ilu ti o ti di ahoro,ninu awon ile ti eniyan ko gbodo gbe,awon ile ti yoo pada di okiti alapa.Gbogbo awon olusona ti won yan lati maa so enu ona abawole je igba o le mejila (212). A ko oruko won sinu iwe gege bi idile won, ni agbegbe won. Dafidi ati Samueli ariran, ni won fi won si ipo pataki naa. Gbo tiwa, Olorun mi, siju wo wa, bi awa ati ilu ti a n pe oruko re mo, ti wa ninu isodahoro. Ki i se nitori ododo wa ni a se n gbadura si o, sugbon nitori pe alaaanu ni o. Sugbon Isaaki dahun pe, “Aburo re ti wa pelu etan, o si ti gba ire re lo.”Oga re ba pe e, o so fun un pe, ‘Iru iroyin wo ni mo n gbo nipa re yii? Siro ise re bi omo-odo, nitori n oo da o duro lenu ise.’ Jakobu nifee Rakeli, nitori naa, o so fun Labani pe, “N oo sin o ni odun meje nitori Rakeli, omo re kekere.”Abi ki i se lati enu Oga Ogoni rere ati buruku ti n jade?Intemperate dandyism lands a youth in a creditor's farm as a pawn.
Ṣugbọn OLUWA Ọlọrun yín ni kí ẹ súnmọ́ gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe títí di òní. Mijamini, Maadaya, ati Biliga, Èmi, Paulu, ni mo fi ọwọ́ ara mi kọ ọ́ pé, n óo san án pada fún ọ. Kò tún nílò kí n sọ fún ọ pé ìwọ fúnrarẹ, o jẹ mí ní gbèsè ara rẹ. Ó ní, “Ẹ kò gbọdọ̀ fọwọ́ kan ẹni àmìòróró mi,ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe àwọn wolii mi níbi.” Ibi tí o bá kú sí, ni èmi náà yóo kú sí; níbẹ̀ ni wọn yóo sì sin mí sí pẹlu. Ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí ọ yìí, kí OLUWA jẹ́ kí ohun tí ó burú jù bẹ́ẹ̀ lọ bá mi, bí mo bá jẹ́ kí ohunkohun yà mí kúrò lẹ́yìn rẹ, ìbáà tilẹ̀ jẹ́ ikú.”Ẹ̀mí èṣù náà bá gbo ọkunrin náà jìgìjìgì, ó kígbe tòò, ó sì jáde kúrò ninu ọkunrin náà. Nígbà náà ni gbogbo àwọn ará ilẹ̀ Midiani ati àwọn ará ilẹ̀ Amaleki ati àwọn ará ilẹ̀ tí ó wà ní ìhà ìlà oòrùn kó ara wọn jọ, wọ́n la odò Jọdani kọjá, wọ́n sì pàgọ́ wọn sí àfonífojì Jesireeli. Ẹ ranti iṣẹ́ ribiribi tí ó ti ṣe,ẹ ranti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ ati ìdájọ́ rẹ̀.The toad tells the snake to follow it, for it does not fight except by the roadside.
Sugbon OLUWA Olorun yin ni ki e sunmo gege bi e ti se titi di oni. Mijamini, Maadaya, ati Biliga, Emi, Paulu, ni mo fi owo ara mi ko o pe, n oo san an pada fun o. Ko tun nilo ki n so fun o pe iwo funrare, o je mi ni gbese ara re. O ni, “E ko gbodo fowo kan eni amiororo mi,e ko si gbodo se awon wolii mi nibi.” Ibi ti o ba ku si, ni emi naa yoo ku si; nibe ni won yoo si sin mi si pelu. Ohun ti o sele si o yii, ki OLUWA je ki ohun ti o buru ju bee lo ba mi, bi mo ba je ki ohunkohun ya mi kuro leyin re, ibaa tile je iku.”Emi esu naa ba gbo okunrin naa jigijigi, o kigbe too, o si jade kuro ninu okunrin naa. Nigba naa ni gbogbo awon ara ile Midiani ati awon ara ile Amaleki ati awon ara ile ti o wa ni iha ila oorun ko ara won jo, won la odo Jodani koja, won si pago won si afonifoji Jesireeli. E ranti ise ribiribi ti o ti se,e ranti ise iyanu re ati idajo re.The toad tells the snake to follow it, for it does not fight except by the roadside.
Àjẹ́kù là ńmayo.
Ajeku la nmayo.
Àwọn mejeeji dá majẹmu níwájú OLUWA; Dafidi dúró ní Horeṣi, Jonatani sì pada sílé. Ẹni tí ó bá jẹ́ olóòótọ́ eniyan, yóo máa rìn láìfòyà,ṣugbọn àṣírí alágàbàgebè yóo tú.The elephant is not among the ranks of animals one lies in ambush for.
Awon mejeeji da majemu niwaju OLUWA; Dafidi duro ni Horesi, Jonatani si pada sile. Eni ti o ba je oloooto eniyan, yoo maa rin laifoya,sugbon asiri alagabagebe yoo tu.The elephant is not among the ranks of animals one lies in ambush for.
Èyí ni pé òfin jẹ́ olùtọ́ wa títí Kristi fi dé, kí á lè dá wa láre nípa igbagbọ. Ó dójúti àwọn olóyè,ó tú àmùrè àwọn alágbára.Nítorí nǹkan àṣírí kan tíí máa fa rúkèrúdò ti bẹ̀rẹ̀ sí ṣiṣẹ́, ṣugbọn ẹni tí ó ń ká a lọ́wọ́ kò wà, kò ì kúrò lọ́nà. OLUWA pàápàá sì ti sọ lónìí pé, eniyan òun ni ọ́, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí fún ọ, ati pé kí o pa gbogbo òfin òun mọ́. Bẹ́ẹ̀ ni Eleasari alufaa ati Joṣua ọmọ Nuni ati àwọn àgbààgbà ninu ẹ̀yà àwọn eniyan Israẹli ṣe ṣẹ́ gègé láti pín ilẹ̀ náà ní Ṣilo níwájú OLUWA, ní ẹnu ọ̀nà àgọ́ ìpàdé; wọ́n sì parí pípín ilẹ̀ náà.Èyí rí bẹ́ẹ̀ kí ọ̀rọ̀ tí wolii Aisaya sọ lè ṣẹ pé:Gbogbo pákó tí a fi dárà sí ara ògirini wọ́n fi àáké ati òòlù fọ́.Nígbà tí wọ́n bá di ẹni aadọta ọdún, iṣẹ́ wọn ninu Àgọ́ Àjọ yóo dópin. Wọn kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ níbẹ̀ mọ́, Ọlọrun, mímọ́ ni ọ̀nà rẹ;oriṣa wo ni ó tó Ọlọrun wa?Jọ̀wọ́ fún wa ní ààyè láti lọ gé igi ní etí odò Jọdani láti fi kọ́ ilé mìíràn tí a óo máa gbé.”Eliṣa dáhùn pé, “Ó dára, ẹ máa lọ.”OLUWA yóo da oówo burúkú bò yín lẹ́sẹ̀ ati lórúnkún, yóo burú tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò ní lè wò yín sàn. Láti àtẹ́lẹsẹ̀ yín títí dé àtàrí yín kìkì oówo ni yóo jẹ́.Lẹ́yìn ọdún keji tí àìsàn náà tí ń ṣe é, ìfun rẹ̀ tú síta, ó sì kú ninu ọpọlọpọ ìrora. Wọn kò dá iná ẹ̀yẹ fún un gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti máa ń ṣe níbi ìsìnkú àwọn baba rẹ̀.Ó dé ibi ihò àpáta kan, ó sì sùn níbẹ̀ mọ́jú ọjọ́ keji.OLUWA bá a sọ̀rọ̀, ó bi í pé, “Elija, kí ni ò ń ṣe níhìn-ín?”“Wo Behemoti, ẹran ńlá inú omi,tí mo dá gẹ́gẹ́ bí mo ti dá ọ,koríko ni ó ń jẹ bíi mààlúù!Jehudi, Beneberaki, Gati Rimoni Wọ́n gbé àpótí OLUWA sinu kẹ̀kẹ́ ẹrù náà, pẹlu àpótí tí wọ́n kó àwọn èkúté wúrà ati kókó ọlọ́yún wúrà náà sí. Àwọn ọ̀pá náà gùn tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi lè rí orí wọn láti ibi mímọ́ jùlọ, ṣugbọn wọn kò lè rí wọn láti ìta. Wọ́n wà níbẹ̀ títí di òní olónìí. OLUWA yóo rán àjàkálẹ̀ àrùn sí ọ títí tí yóo fi pa ọ́ run patapata, lórí ilẹ̀ tí ò ń wọ̀ lọ láti gbà. Nígbà tí ó ti di ọdún kẹta tí ó ti dó ti Samaria, ó ṣẹgun rẹ̀. Èyí jẹ́ ọdún kẹfa tí Hesekaya jọba, ati ọdún kẹsan-an tí Hoṣea jọba. A di gàárì sílẹ̀ ewúrẹ́ ńyọjú; ẹrù ìran rẹ̀ ni?
Eyi ni pe ofin je oluto wa titi Kristi fi de, ki a le da wa lare nipa igbagbo. O dojuti awon oloye,o tu amure awon alagbara.Nitori nnkan asiri kan tii maa fa rukerudo ti bere si sise, sugbon eni ti o n ka a lowo ko wa, ko i kuro lona. OLUWA paapaa si ti so lonii pe, eniyan oun ni o, gege bi o ti seleri fun o, ati pe ki o pa gbogbo ofin oun mo. Bee ni Eleasari alufaa ati Josua omo Nuni ati awon agbaagba ninu eya awon eniyan Israeli se se gege lati pin ile naa ni Silo niwaju OLUWA, ni enu ona ago ipade; won si pari pipin ile naa.Eyi ri bee ki oro ti wolii Aisaya so le se pe:Gbogbo pako ti a fi dara si ara ogirini won fi aake ati oolu fo.Nigba ti won ba di eni aadota odun, ise won ninu Ago Ajo yoo dopin. Won ko gbodo se ise nibe mo, Olorun, mimo ni ona re;orisa wo ni o to Olorun wa?Jowo fun wa ni aaye lati lo ge igi ni eti odo Jodani lati fi ko ile miiran ti a oo maa gbe.”Elisa dahun pe, “O dara, e maa lo.”OLUWA yoo da oowo buruku bo yin lese ati lorunkun, yoo buru tobee ti enikeni ko ni le wo yin san. Lati atelese yin titi de atari yin kiki oowo ni yoo je.Leyin odun keji ti aisan naa ti n se e, ifun re tu sita, o si ku ninu opolopo irora. Won ko da ina eye fun un gege bi won ti maa n se nibi isinku awon baba re.O de ibi iho apata kan, o si sun nibe moju ojo keji.OLUWA ba a soro, o bi i pe, “Elija, ki ni o n se nihin-in?”“Wo Behemoti, eran nla inu omi,ti mo da gege bi mo ti da o,koriko ni o n je bii maaluu!Jehudi, Beneberaki, Gati Rimoni Won gbe apoti OLUWA sinu keke eru naa, pelu apoti ti won ko awon ekute wura ati koko oloyun wura naa si. Awon opa naa gun tobee ti won fi le ri ori won lati ibi mimo julo, sugbon won ko le ri won lati ita. Won wa nibe titi di oni olonii. OLUWA yoo ran ajakale arun si o titi ti yoo fi pa o run patapata, lori ile ti o n wo lo lati gba. Nigba ti o ti di odun keta ti o ti do ti Samaria, o segun re. Eyi je odun kefa ti Hesekaya joba, ati odun kesan-an ti Hosea joba. A di gaari sile ewure nyoju; eru iran re ni?
Ilẹ̀ yóo sì dáhùn adura ọkà, ati ti waini ati ti òróró.Àwọn náà óo sì dáhùn adura Jesireeli.A óo waasu ìyìn rere ìjọba yìí ní gbogbo ayé gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí sí gbogbo orílẹ̀-èdè. Lẹ́yìn náà ni òpin yóo dé.Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, tí oòrùn wọ̀, àwọn eniyan bẹ̀rẹ̀ sí gbé gbogbo àwọn tí ara wọn kò dá ati àwọn tí wọ́n ní ẹ̀mí èṣù wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀. Nítòótọ́ Ọlọrun óo bá ọ kanlẹ̀,yóo gbá ọ mú, yóo sì fà ọ́ já kúrò ninu ilé rẹ;yóo fà ọ́ tu kúrò lórí ilẹ̀ alààyè.Ìlú tí kò gba ìmọ̀ràn ati ìbáwí, tí kò gbẹ́kẹ̀lé OLUWA, tí kò sì súnmọ́ Ọlọrun rẹ̀. Gideoni mú mẹ́wàá ninu àwọn iranṣẹ rẹ̀, ó sì ṣe bí OLUWA ti ní kí ó ṣe, ṣugbọn kò lè ṣe é lọ́sàn-án, nítorí ẹ̀rù àwọn ará ilé ati àwọn ará ìlú rẹ̀ ń bà á, nítorí náà lóru ni ó ṣe é.Àjànàkú kúrò lẹ́ran à ńgọ dé.
Ile yoo si dahun adura oka, ati ti waini ati ti ororo.Awon naa oo si dahun adura Jesireeli.A oo waasu iyin rere ijoba yii ni gbogbo aye gege bi eri si gbogbo orile-ede. Leyin naa ni opin yoo de.Nigba ti o di irole, ti oorun wo, awon eniyan bere si gbe gbogbo awon ti ara won ko da ati awon ti won ni emi esu wa si odo re. Nitooto Olorun oo ba o kanle,yoo gba o mu, yoo si fa o ja kuro ninu ile re;yoo fa o tu kuro lori ile alaaye.Ilu ti ko gba imoran ati ibawi, ti ko gbekele OLUWA, ti ko si sunmo Olorun re. Gideoni mu mewaa ninu awon iranse re, o si se bi OLUWA ti ni ki o se, sugbon ko le se e losan-an, nitori eru awon ara ile ati awon ara ilu re n ba a, nitori naa loru ni o se e.Ajanaku kuro leran a ngo de.
Ọlọ́gbọ́n ọmọ a máa mú inú baba rẹ̀ dùn,ṣugbọn òmùgọ̀ ọmọ níí kẹ́gàn ìyá rẹ̀.Wọ́n bá mú wọn, wọ́n tì wọ́n mọ́lé títí di ọjọ́ keji, nítorí ilẹ̀ ti ṣú. Leaving-remnants is the indicator of satiation.
Ologbon omo a maa mu inu baba re dun,sugbon omugo omo nii kegan iya re.Won ba mu won, won ti won mole titi di ojo keji, nitori ile ti su. Leaving-remnants is the indicator of satiation.
Nígbà tí gbogbo Israẹli rí i pé, ọba kò gbọ́ tiwọn, wọ́n dá a lóhùn pé, “Kí ló kàn wá pẹlu ìdílé Dafidi?Kí ló dà wá pọ̀ pẹlu ọmọ Jese?Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ pada sílé yín,kí Dafidi máa bojútó ilé rẹ̀!”Ẹnikẹ́ni kò mọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọ̀la; ta ló lè sọ fún eniyan bí yóo ṣe ṣẹlẹ̀? Isaaki bá wí tìfura-tìfura pé, “Súnmọ́ mi, kí n fọwọ́ kàn ọ́, kí n lè mọ̀ bóyá Esau ọmọ mi ni ọ́ lóòótọ́.” Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọ láàrin ara wọn pé, “Nítorí a kò ní burẹdi ni.”Abidoni ni àkọ́bí rẹ̀, lẹ́yìn náà ni ó bí: Suri, Kiṣi, Baali, Neri, ati Nadabu; Ẹ gbé àsíá kan sókè, ẹ gbé e ti odi Babiloni;ẹ ṣe ìsénà tí ó lágbára.Ẹ fi àwọn aṣọ́nà sí ipò wọn;ẹ dira fún àwọn kan, kí wọn sápamọ́,nítorí OLUWA ti pinnu, ó sì ti ṣe ohun tí ó sọ nípa àwọn ará Babiloni.Olè ati ọlọ́ṣà ni gbogbo àwọn tí wọ́n ti wá ṣiwaju mi. Ṣugbọn àwọn aguntan kò gbọ́ ti wọn. “Bí mo ti ń wò ó, mo rí i ti ìwo yìí ń bá àwọn eniyan mímọ́ jà, tí ó sì ń ṣẹgun wọn, A sharp object is not something to grab for; “it is” a-thing-that-pierces-one's-hand-like-a-sharp-instrument.
Nigba ti gbogbo Israeli ri i pe, oba ko gbo tiwon, won da a lohun pe, “Ki lo kan wa pelu idile Dafidi?Ki lo da wa po pelu omo Jese?Eyin omo Israeli, e pada sile yin,ki Dafidi maa bojuto ile re!”Enikeni ko mo ohun ti yoo sele leyin ola; ta lo le so fun eniyan bi yoo se sele? Isaaki ba wi tifura-tifura pe, “Sunmo mi, ki n fowo kan o, ki n le mo boya Esau omo mi ni o loooto.” Won bere si so laarin ara won pe, “Nitori a ko ni buredi ni.”Abidoni ni akobi re, leyin naa ni o bi: Suri, Kisi, Baali, Neri, ati Nadabu; E gbe asia kan soke, e gbe e ti odi Babiloni;e se isena ti o lagbara.E fi awon asona si ipo won;e dira fun awon kan, ki won sapamo,nitori OLUWA ti pinnu, o si ti se ohun ti o so nipa awon ara Babiloni.Ole ati olosa ni gbogbo awon ti won ti wa siwaju mi. Sugbon awon aguntan ko gbo ti won. “Bi mo ti n wo o, mo ri i ti iwo yii n ba awon eniyan mimo ja, ti o si n segun won, A sharp object is not something to grab for; “it is” a-thing-that-pierces-one's-hand-like-a-sharp-instrument.
Mose bá gun orí òkè náà lọ, ìkùukùu sì bo orí òkè náà. Ikọkandinlogun mú Maloti, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila. Mò ń tọ ọ̀nà rẹ tààrà;ẹsẹ̀ mi kò sì yọ̀.“Mo bẹ̀ ọ́ OLUWA, ranti bí mo ti sìn ọ́ pẹlu òtítọ́ ati ọkàn pípé, ati bí mo ti ń ṣe ohun tí o fẹ́.” Ó sì sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn.Ẹ̀jẹ̀ àwọn tí ó pa yóo wà lórí rẹ̀ ati lórí àwọn arọmọdọmọ rẹ̀ títí lae, ṣugbọn OLUWA yóo fún Dafidi ati àwọn arọmọdọmọ rẹ̀ ati ilé rẹ̀ ati ìjọba rẹ̀ ní alaafia títí lae.”Ahira ọmọ Enani ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Nafutali. OLUWA Ọlọrun ní, “Ní ọjọ́ tí mo bá wẹ̀ yín mọ́ kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ yín, n óo jẹ́ kí àwọn eniyan máa gbé inú àwọn ìlú yín, n óo sì mú kí wọ́n tún àwọn ibi tí ó wó lulẹ̀ kọ́. Ewúrẹ́ ò lè rí ewé ọdán òkè fi ṣe nǹkan.
Mose ba gun ori oke naa lo, ikuukuu si bo ori oke naa. Ikokandinlogun mu Maloti, oun ati awon omo re okunrin, ati awon arakunrin re je mejila. Mo n to ona re taara;ese mi ko si yo.“Mo be o OLUWA, ranti bi mo ti sin o pelu otito ati okan pipe, ati bi mo ti n se ohun ti o fe.” O si sokun teduntedun.Eje awon ti o pa yoo wa lori re ati lori awon aromodomo re titi lae, sugbon OLUWA yoo fun Dafidi ati awon aromodomo re ati ile re ati ijoba re ni alaafia titi lae.”Ahira omo Enani ni yoo je olori lati inu eya Nafutali. OLUWA Olorun ni, “Ni ojo ti mo ba we yin mo kuro ninu ese yin, n oo je ki awon eniyan maa gbe inu awon ilu yin, n oo si mu ki won tun awon ibi ti o wo lule ko. Ewure o le ri ewe odan oke fi se nnkan.
Hana bá dá a lóhùn pé, “Jẹ́ kí èmi, iranṣẹbinrin rẹ, bá ojurere rẹ pàdé.” Ó bá dìde, ó jẹun, ó dárayá, kò sì banújẹ́ mọ́.Àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn ìdílé Saulu, ati àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn ìdílé Dafidi bá ara wọn jagun fún ìgbà pípẹ́. Bí agbára Dafidi ti ń pọ̀ sí i, bẹ́ẹ̀ ni agbára àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn Saulu ń dínkù. Ní àkókò kan náà, Tatenai, gomina agbègbè òdìkejì odò ati Ṣetari Bosenai ati gbogbo àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn wá sí ọ̀dọ̀ wọn, wọ́n bi wọ́n léèrè pé: “Ta ló fun yín láṣẹ láti kọ́ tẹmpili yìí ati láti dá àwọn nǹkan inú rẹ̀ pada sibẹ? Gbólóhùn kan-án ba ọ̀rọ̀ jẹ́; gbólóhùn kan-án tún ọ̀rọ̀ ṣe.
Hana ba da a lohun pe, “Je ki emi, iransebinrin re, ba ojurere re pade.” O ba dide, o jeun, o daraya, ko si banuje mo.Awon ti won wa leyin idile Saulu, ati awon ti won wa leyin idile Dafidi ba ara won jagun fun igba pipe. Bi agbara Dafidi ti n po si i, bee ni agbara awon ti won wa leyin Saulu n dinku. Ni akoko kan naa, Tatenai, gomina agbegbe odikeji odo ati Setari Bosenai ati gbogbo awon elegbe won wa si odo won, won bi won leere pe: “Ta lo fun yin lase lati ko tempili yii ati lati da awon nnkan inu re pada sibe? Gbolohun kan-an ba oro je; gbolohun kan-an tun oro se.
“Ọlọrun ti fi àṣẹ sí i pé, lẹ́yìn aadọrin ọdún lọ́nà meje ni òun óo tó dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan rẹ ati ti ìlú mímọ́ rẹ jì wọ́n, tí òun óo ṣe ètùtù fún ìwà burúkú wọn, tí òun óo mú òdodo ainipẹkun ṣẹ, tí òun óo fi èdìdì di ìran ati àsọtẹ́lẹ̀ náà, tí òun óo sì fi òróró ya Ilé Mímọ́ Jùlọ rẹ̀ sọ́tọ̀. Nítorí náà, ẹni tí ó bá rò pé òun dúró kí ó ṣọ́ra kí ó má baà ṣubú. Kí ni eniyan jẹ́, tí ó fi lè mọ́ níwájú Ọlọrun?Kí ni ẹnikẹ́ni tí obinrin bí já mọ́, tí ó fi lè jẹ́ olódodo?Ẹ̀rù yín ń bà mí pé kí gbogbo làálàá mi lórí yín má wá jẹ́ lásán!Ẹ óo ṣe gbogbo nǹkan wọnyi kí ẹ lè fi orí gba ẹ̀bi ikú gbogbo eniyan rere tí ẹ ti ta ẹ̀jẹ̀ wọn sílẹ̀; ohun tí ó ṣẹ̀ láti orí Abeli, ẹni rere títí fi dé orí Sakaraya, ọmọ Berekaya, tí ẹ pa láàrin àgọ́ mímọ́ ati pẹpẹ ìrúbọ. láti gbọ́ ìkérora àwọn ìgbèkùn,ati láti dá àwọn tí a dájọ́ ikú fún sílẹ̀.Ọba Sedekaya rán Jehukali, ọmọ Ṣelemaya, ati Sefanaya, alufaa, ọmọ Maaseaya, sí Jeremaya wolii, pé kí ó jọ̀wọ́ bá àwọn gba adura sí OLUWA Ọlọrun. Jafileti bí ọmọ mẹta: Pasaki, Bimihali, ati Aṣifatu.Wọ́n ń lé ọpọlọpọ ẹ̀mí èṣù jáde, wọ́n ń fi òróró pa ọpọlọpọ aláìsàn lára, wọ́n sì ń mú wọn lára dá. Labani fi Silipa ẹrubinrin rẹ̀ fún Lea pé kí ó máa ṣe iranṣẹ fún un. Kí oore-ọ̀fẹ́ Oluwa Jesu Kristi kí ó wà pẹlu ẹ̀mí yín.Ninu Kristi ni Ọlọrun fi gbogbo ìṣúra ọgbọ́n ati ìmọ̀ pamọ́ sí.Whoever leaps up decapitates dance.
“Olorun ti fi ase si i pe, leyin aadorin odun lona meje ni oun oo to dari ese awon eniyan re ati ti ilu mimo re ji won, ti oun oo se etutu fun iwa buruku won, ti oun oo mu ododo ainipekun se, ti oun oo fi edidi di iran ati asotele naa, ti oun oo si fi ororo ya Ile Mimo Julo re soto. Nitori naa, eni ti o ba ro pe oun duro ki o sora ki o ma baa subu. Ki ni eniyan je, ti o fi le mo niwaju Olorun?Ki ni enikeni ti obinrin bi ja mo, ti o fi le je olododo?Eru yin n ba mi pe ki gbogbo laalaa mi lori yin ma wa je lasan!E oo se gbogbo nnkan wonyi ki e le fi ori gba ebi iku gbogbo eniyan rere ti e ti ta eje won sile; ohun ti o se lati ori Abeli, eni rere titi fi de ori Sakaraya, omo Berekaya, ti e pa laarin ago mimo ati pepe irubo. lati gbo ikerora awon igbekun,ati lati da awon ti a dajo iku fun sile.Oba Sedekaya ran Jehukali, omo Selemaya, ati Sefanaya, alufaa, omo Maaseaya, si Jeremaya wolii, pe ki o jowo ba awon gba adura si OLUWA Olorun. Jafileti bi omo meta: Pasaki, Bimihali, ati Asifatu.Won n le opolopo emi esu jade, won n fi ororo pa opolopo alaisan lara, won si n mu won lara da. Labani fi Silipa erubinrin re fun Lea pe ki o maa se iranse fun un. Ki oore-ofe Oluwa Jesu Kristi ki o wa pelu emi yin.Ninu Kristi ni Olorun fi gbogbo isura ogbon ati imo pamo si.Whoever leaps up decapitates dance.
Orin tí Hesekaya ọba Juda kọ sílẹ̀ nígbà tí ó ṣàìsàn tí Ọlọrun sì wò ó sàn nìyí:14. Ìwọ kò ha rí i, tí ô ẹni tí ô n kọ fún un) bá kò, tò sì pẹ̀hìndà,
Orin ti Hesekaya oba Juda ko sile nigba ti o saisan ti Olorun si wo o san niyi:14. Iwo ko ha ri i, ti o eni ti o n ko fun un) ba ko, to si pehinda,
15. Ṣé òun kò ha mọ pé Allah rí ohun tí òun n ṣe ni?
15. Se oun ko ha mo pe Allah ri ohun ti oun n se ni?
16. Kíyẹ̀sí i! Tí kò bá ṣíwọ, dájúdájú, Awa Ôô fi ìrun iwájú rẹ̀ fà a,
16. Kiyesi i! Ti ko ba siwo, dajudaju, Awa Oo fi irun iwaju re fa a,
17. Ìrun iwájú tí ô fi fì purò, tí ô fi n dẹ̀sẹ̀.
17. Irun iwaju ti o fi fi puro, ti o fi n dese.
14. Nígbà náà, kí 0 pe àwọn ẹlẹgbẹ rẹ̀,
14. Nigba naa, ki 0 pe awon elegbe re,
19. Àwa náà yòò pe àwọn Olùṣò iná (lati sọ Ọ sínú iná).
19. Awa naa yoo pe awon Oluso ina (lati so O sinu ina).
20. Rárá o! má ṣe tẹ̀lé e, ṣùgbọn kí o foríbalẹ̀ (fún Allah) kí o si
20. Rara o! ma se tele e, sugbon ki o foribale (fun Allah) ki o si
máa súnmọ Ọn.
maa sunmo On.
1. Ní Orúkọ Allah, Olôore ẹ̀f€, Alaàánú jùlọ.
1. Ni Oruko Allah, Oloore ef€, Alaaanu julo.
2. Dájúdájú, A sò ò kalẹ̀ ní Òru Abiyì náà.
2. Dajudaju, A so o kale ni Oru Abiyi naa.
3. Kí ni yòò mú ọ mọ Òru Abiyì náà?
3. Ki ni yoo mu o mo Oru Abiyi naa?
4. Òru Abiyì náà, dára ju ẹgbẹ̀rún soṣù lọ.Wọ́n ń sọ̀rọ̀ burúkú sí wa, ṣugbọn àwa ń sọ̀rọ̀ ìwúrí. A di ohun ẹ̀sín fún gbogbo ayé. A di pàǹtí fún gbogbo eniyan títí di bí a ti ń sọ̀rọ̀ yìí.Orúkọ àwọn alákòóso mejeejila ati agbègbè tí olukuluku wọn ń mójú tó nìwọ̀nyí: Benhuri ní ń ṣe àkóso agbègbè olókè Efuraimu; O ní kí n tẹ́tí sílẹ̀,nígbà tí o bá ń sọ̀rọ̀,kí n sì dáhùn nígbà tí o bá bèèrè nǹkan lọ́wọ́ mi.Nítorí Ọlọrun kì í ṣe alaiṣootọ, tí yóo fi gbàgbé iṣẹ́ yín ati ìfẹ́ yín tí ẹ fihàn sí orúkọ rẹ̀, nígbà tí ẹ ṣe iṣẹ́ iranṣẹ fún àwọn onigbagbọ, bí ẹ ti tún ń ṣe nisinsinyii. Lẹ́yìn náà ó pàṣẹ fún Uraya alufaa, ó ní, “Máa lo pẹpẹ ìrúbọ tí ó tóbi yìí fún ẹbọ sísun àárọ̀ ati ẹbọ ohun jíjẹ ìrọ̀lẹ́, ati fún ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ ti ọba, ati fún ẹbọ ohun jíjẹ ati ti ohun mímu ti àwọn eniyan. Kí o sì máa da ẹ̀jẹ̀ gbogbo àwọn ẹran tí wọ́n bá pa fún ìrúbọ sí orí rẹ̀. Ṣugbọn gbé pẹpẹ ìrúbọ idẹ tọ̀hún sọ́tọ̀ fún mi kí n lè máa lò ó láti wádìí ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ OLUWA.” OLUWA fún Solomoni ní ọgbọ́n gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ̀, alaafia sì wà láàrin òun ati Hiramu, àwọn mejeeji sì bá ara wọn dá majẹmu.Ó sọ fún àwọn ọmọ Lefi tí wọn ń kọ́ àwọn ọmọ Israẹli, tí wọ́n sì jẹ́ mímọ́ pé, “Ẹ gbé Àpótí mímọ́ náà sinu ilé tí Solomoni ọmọ Dafidi, ọba Israẹli kọ́. Ẹ kò ní máa gbé e lé èjìká kiri mọ́. Ṣugbọn kí ẹ máa ṣiṣẹ́ fún OLUWA Ọlọrun, ati fún gbogbo eniyan Israẹli. “Ní ọjọ́ kẹwaa oṣù keje yìí, ẹ óo máa ní àpèjọ mímọ́, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ohunkohun bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan. Àwọn àjèjì láti inú orílẹ̀-èdè, tí ó burú jùlọ, yóo gé e lulẹ̀, wọn yóo sì fi í sílẹ̀. Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ yóo bọ́ sílẹ̀ lórí àwọn òkè ati ní àwọn àfonífojì, igi rẹ̀ yóo sì wà nílẹ̀ káàkiri ní gbogbo ipadò ilẹ̀ náà. Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yóo kúrò lábẹ́ òjìji rẹ̀, wọn yóo sì fi sílẹ̀. Yóo gba ilẹ̀ oko yín tí ó dára jùlọ ati ọgbà àjàrà ati ti olifi yín, yóo sì fi fún àwọn iranṣẹ rẹ̀. Mo ti fi àwọn ọmọ Lefi fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ láti inú àwọn ọmọ Israẹli, láti máa ṣe iṣẹ́ ìsìn ninu Àgọ́ Àjọ ati láti máa ṣe ètùtù fún àwọn ọmọ Israẹli, kí àjàkálẹ̀ àrùn má baà bẹ́ sílẹ̀ láàrin wọn nígbà tí wọn bá súnmọ́ ibi mímọ́.”Láti fi òdodo rẹ̀ hàn ní ìgbà ìsinsin yìí: kí ó lè jẹ́ olódodo àti olùdáláre ẹni tí ó gba Jesu gbọ́.Nítorí gbogbo èyí, mo fi lé àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́, àwọn ará Asiria tí ó ń ṣẹ́jú sí. Àwọn obinrin gba àwọn eniyan wọn tí wọ́n ti kú pada lẹ́yìn tí a ti jí wọn dìde kúrò ninu òkú. A dá àwọn mìíràn lóró títí wọ́n fi kú. Wọn kò pé kí á dá wọn sílẹ̀, nítorí kí wọ́n lè gba ajinde tí ó dára jùlọ. Mo wá rí obinrin náà tí ó ti mu ẹ̀jẹ̀ àwọn eniyan Ọlọrun ní àmuyó, pẹlu ẹ̀jẹ̀ àwọn tí wọ́n jẹ́rìí igbagbọ ninu Jesu.Ìyanu ńlá ni ó jẹ́ fún mi nígbà tí mo rí obinrin náà. Ní ọ̀sán gangan ọjọ́ kan, OLUWA fara han Abrahamu bí ó ti jókòó ní ẹnu ọ̀nà àgọ́ rẹ̀, lẹ́bàá igi Oaku ti Mamure. “Bí òjò ati yìnyín, tí ń rọ̀ láti ojú ọ̀run, tí wọn kì í pada sibẹ mọ́,ṣugbọn tí wọn ń bomi rin ilẹ̀,tí ń mú kí nǹkan hù jáde;kí àgbẹ̀ lè rí èso gbìn,kí eniyan sì rí oúnjẹ jẹ.Ó sọ omi wọn di ẹ̀jẹ̀,ó sì mú kí ẹja wọn kú.Lẹ́yìn èyí, àwọn ọmọ Israẹli wí fún Gideoni pé, “Máa jọba lórí wa, ìwọ ati ọmọ rẹ, ati àwọn ọmọ ọmọ rẹ pẹlu, nítorí pé ìwọ ni o gbà wá lọ́wọ́ àwọn ará Midiani.”Wọ́n bá pada sí Sifi ṣáájú Saulu. Ṣugbọn Dafidi ati àwọn ọkunrin rẹ̀ ti wà ní aṣálẹ̀ Maoni tí ó wà ní Araba lápá ìhà gúsù Jeṣimoni. Nítorí bí eniyan bá lè di ajogún nípa òfin, a jẹ́ pé kì í tún ṣe ìlérí mọ́. Bẹ́ẹ̀ sì ni nípa ìlérí ni Ọlọrun fún Abrahamu ní ogún. Nítorí pé, ẹ̀yin mejeeji ni ẹ kò hùwà òtítọ́ sí mi láàrin àwọn ọmọ Israẹli, nígbà tí ẹ wà ní odò Meriba Kadeṣi, ní aṣálẹ̀ Sini. Ẹ tàbùkù mi lójú gbogbo àwọn eniyan, ẹ kò bọ̀wọ̀ fún mi gẹ́gẹ́ bí ẹni mímọ́ níwájú àwọn eniyan náà. Ọmọ iná là ńrán síná.
4. Oru Abiyi naa, dara ju egberun sosu lo.Won n soro buruku si wa, sugbon awa n soro iwuri. A di ohun esin fun gbogbo aye. A di panti fun gbogbo eniyan titi di bi a ti n soro yii.Oruko awon alakooso mejeejila ati agbegbe ti olukuluku won n moju to niwonyi: Benhuri ni n se akoso agbegbe oloke Efuraimu; O ni ki n teti sile,nigba ti o ba n soro,ki n si dahun nigba ti o ba beere nnkan lowo mi.Nitori Olorun ki i se alaisooto, ti yoo fi gbagbe ise yin ati ife yin ti e fihan si oruko re, nigba ti e se ise iranse fun awon onigbagbo, bi e ti tun n se nisinsinyii. Leyin naa o pase fun Uraya alufaa, o ni, “Maa lo pepe irubo ti o tobi yii fun ebo sisun aaro ati ebo ohun jije irole, ati fun ebo sisun ati ebo ohun jije ti oba, ati fun ebo ohun jije ati ti ohun mimu ti awon eniyan. Ki o si maa da eje gbogbo awon eran ti won ba pa fun irubo si ori re. Sugbon gbe pepe irubo ide tohun soto fun mi ki n le maa lo o lati wadii oro lowo OLUWA.” OLUWA fun Solomoni ni ogbon gege bi ileri re, alaafia si wa laarin oun ati Hiramu, awon mejeeji si ba ara won da majemu.O so fun awon omo Lefi ti won n ko awon omo Israeli, ti won si je mimo pe, “E gbe Apoti mimo naa sinu ile ti Solomoni omo Dafidi, oba Israeli ko. E ko ni maa gbe e le ejika kiri mo. Sugbon ki e maa sise fun OLUWA Olorun, ati fun gbogbo eniyan Israeli. “Ni ojo kewaa osu keje yii, e oo maa ni apejo mimo, e ko gbodo je ohunkohun bee ni e ko gbodo se ise kankan. Awon ajeji lati inu orile-ede, ti o buru julo, yoo ge e lule, won yoo si fi i sile. Awon eka re yoo bo sile lori awon oke ati ni awon afonifoji, igi re yoo si wa nile kaakiri ni gbogbo ipado ile naa. Gbogbo awon orile-ede yoo kuro labe ojiji re, won yoo si fi sile. Yoo gba ile oko yin ti o dara julo ati ogba ajara ati ti olifi yin, yoo si fi fun awon iranse re. Mo ti fi awon omo Lefi fun Aaroni ati awon omo re gege bi ore lati inu awon omo Israeli, lati maa se ise isin ninu Ago Ajo ati lati maa se etutu fun awon omo Israeli, ki ajakale arun ma baa be sile laarin won nigba ti won ba sunmo ibi mimo.”Lati fi ododo re han ni igba isinsin yii: ki o le je olododo ati oludalare eni ti o gba Jesu gbo.Nitori gbogbo eyi, mo fi le awon ololufe re lowo, awon ara Asiria ti o n seju si. Awon obinrin gba awon eniyan won ti won ti ku pada leyin ti a ti ji won dide kuro ninu oku. A da awon miiran loro titi won fi ku. Won ko pe ki a da won sile, nitori ki won le gba ajinde ti o dara julo. Mo wa ri obinrin naa ti o ti mu eje awon eniyan Olorun ni amuyo, pelu eje awon ti won jerii igbagbo ninu Jesu.Iyanu nla ni o je fun mi nigba ti mo ri obinrin naa. Ni osan gangan ojo kan, OLUWA fara han Abrahamu bi o ti jokoo ni enu ona ago re, lebaa igi Oaku ti Mamure. “Bi ojo ati yinyin, ti n ro lati oju orun, ti won ki i pada sibe mo,sugbon ti won n bomi rin ile,ti n mu ki nnkan hu jade;ki agbe le ri eso gbin,ki eniyan si ri ounje je.O so omi won di eje,o si mu ki eja won ku.Leyin eyi, awon omo Israeli wi fun Gideoni pe, “Maa joba lori wa, iwo ati omo re, ati awon omo omo re pelu, nitori pe iwo ni o gba wa lowo awon ara Midiani.”Won ba pada si Sifi saaju Saulu. Sugbon Dafidi ati awon okunrin re ti wa ni asale Maoni ti o wa ni Araba lapa iha gusu Jesimoni. Nitori bi eniyan ba le di ajogun nipa ofin, a je pe ki i tun se ileri mo. Bee si ni nipa ileri ni Olorun fun Abrahamu ni ogun. Nitori pe, eyin mejeeji ni e ko huwa otito si mi laarin awon omo Israeli, nigba ti e wa ni odo Meriba Kadesi, ni asale Sini. E tabuku mi loju gbogbo awon eniyan, e ko bowo fun mi gege bi eni mimo niwaju awon eniyan naa. Omo ina la nran sina.
Àwọn tí wọn ń lépa wa yáraju idì tí ń fò lójú ọ̀run lọ.Wọ́n ń lé wa lórí òkè,wọ́n sì ba dè wá ninu aṣálẹ̀.“Níbi tí òkú ẹran bá wà, níbẹ̀ ni àwọn gúnnugún yóo péjọ sí.“Wò ó, mo rán angẹli kan ṣiwaju rẹ láti pa ọ́ mọ́ ní ọ̀nà rẹ, ati láti mú ọ wá sí ibi tí mo ti tọ́jú fún ọ. A child is never so careful about eating corn meal that it does not smear the meal on its mouth.
Awon ti won n lepa wa yaraju idi ti n fo loju orun lo.Won n le wa lori oke,won si ba de wa ninu asale.“Nibi ti oku eran ba wa, nibe ni awon gunnugun yoo pejo si.“Wo o, mo ran angeli kan siwaju re lati pa o mo ni ona re, ati lati mu o wa si ibi ti mo ti toju fun o. A child is never so careful about eating corn meal that it does not smear the meal on its mouth.
Bí o bá pa gbogbo òfin tí Ọlọrun fún Israẹli láti ọwọ́ Mose mọ́, o óo ṣe rere. Múra, kí o sì ṣe ọkàn gírí, má bẹ̀rù, má sì ṣe jẹ́ kí àyà fò ọ́. Gbogbo nǹkan yòókù tí Asa ọba ṣe, ati àwọn ìwà akin tí ó hù, ati àwọn ìlú tí ó mọ odi yípo, ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda, ṣugbọn ní ọjọ́ ogbó rẹ̀, nǹkankan mú un lẹ́sẹ̀. Nígbà tí Mose bá àwọn ọmọ Israẹli sọ gbogbo ọ̀rọ̀ wọnyi tán, Abimeleki mú aguntan ati mààlúù ati ẹrukunrin ati ẹrubinrin, ó kó wọn fún Abrahamu, ó sì dá Sara, aya rẹ̀, pada fún un. Ọ̀mọ̀ràn ní ḿmọ oyún ìgbín.
Bi o ba pa gbogbo ofin ti Olorun fun Israeli lati owo Mose mo, o oo se rere. Mura, ki o si se okan giri, ma beru, ma si se je ki aya fo o. Gbogbo nnkan yooku ti Asa oba se, ati awon iwa akin ti o hu, ati awon ilu ti o mo odi yipo, ni a ko sinu Iwe Itan Awon Oba Juda, sugbon ni ojo ogbo re, nnkankan mu un lese. Nigba ti Mose ba awon omo Israeli so gbogbo oro wonyi tan, Abimeleki mu aguntan ati maaluu ati erukunrin ati erubinrin, o ko won fun Abrahamu, o si da Sara, aya re, pada fun un. Omoran ni mmo oyun igbin.
‘Ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn nítorí ọjọ́ burúkú tí ń bọ̀,nítorí ọjọ́ náà súnmọ́lé,ọjọ́ OLUWA ti dé tán,yóo jẹ́ ọjọ́ ìṣúduduati ìparun fún àwọn orílẹ̀-èdè.Òkú Amasa, tí ẹ̀jẹ̀ ti bò, wà ní ojú ọ̀nà gbangba, ẹnikẹ́ni tí ó bá ń kọjá, tí ó bá rí i ń dúró. Nígbà tí ọkunrin tí ó dúró ti òkú náà rí i pé gbogbo eniyan ní ń dúró, ó wọ́ òkú náà kúrò lójú ọ̀nà, sinu igbó, ó sì fi aṣọ bò ó. Ǹjẹ́ inú OLUWA yóo dùn bí mo bá mú ẹgbẹẹgbẹrun aguntan wá, pẹlu ẹgbẹgbaarun-un garawa òróró olifi? Ṣé kí n fi àkọ́bí mi ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ mi, àní kí n fi ọmọ tí mo bí rúbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ mi? Lẹ́yìn náà ni alufaa yóo fi àwọn ẹbọ náà níwájú OLUWA. Mímọ́ ni wọ́n jẹ́ fún alufaa náà, pẹlu àyà tí a fì ati itan tí wọ́n fi rúbọ. Lẹ́yìn èyí, Nasiri náà lè máa mu ọtí waini.Ṣugbọn ẹ̀ ń kẹ́gàn mẹ̀kúnnù. Ṣebí àwọn ọlọ́rọ̀ níí máa fìtínà yín, tí wọn máa ń fà yín lọ sí kóòtù! OLUWA, yóo ti pẹ́ tó?Àní, yóo ti pẹ́ tó tí àwọn eniyan burúkú yóo máa ṣe jàgínní?Nígbà tí Jakọbu ń kú lọ, nípa igbagbọ ni ó fi súre fún ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Josẹfu. Ó ń sin Ọlọrun bí ó ti tẹríba lórí ọ̀pá rẹ̀. Kí ló dé tí eniyan burúkú fi wà láàyè,tí ó di arúgbó, tí ó sì di alágbára?Ṣugbọn ẹ̀ ń lérí, ẹ̀ ń fọ́nnu; irú ìlérí báyìí kò dára.Usaya tún kọ́ àwọn ilé ìṣọ́ ní Jerusalẹmu níbi Ẹnubodè tí ó wà ní igun odi, ati sí ibi Ẹnubodè àfonífojì, ati níbi Ìṣẹ́po Odi. Ó sì mọ odi sí wọn. Ẹ̀ ń bèèrè pé, “Kí ló dé tí kò fi gbà á?” Ìdí rẹ̀ ni pé, OLUWA ni ẹlẹ́rìí majẹmu tí ẹ dá pẹlu aya tí ẹ fẹ́ nígbà èwe yín, tí ẹ sì ṣe aiṣootọ sí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé olùrànlọ́wọ́ yín ni, òun sì ni aya tí ẹ bá dá majẹmu. N óo sì fi àjàkálẹ̀ àrùn ati ikú ogun ṣe ìdájọ́ wọn. N óo rọ òjò yìnyín, iná, ati imí ọjọ́ lé òun, ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀, ati ọpọlọpọ eniyan pupọ tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ lórí. 4. Àyàfi àwọn tò gbàgbò lôdodo
‘E sokun teduntedun nitori ojo buruku ti n bo,nitori ojo naa sunmole,ojo OLUWA ti de tan,yoo je ojo isududuati iparun fun awon orile-ede.Oku Amasa, ti eje ti bo, wa ni oju ona gbangba, enikeni ti o ba n koja, ti o ba ri i n duro. Nigba ti okunrin ti o duro ti oku naa ri i pe gbogbo eniyan ni n duro, o wo oku naa kuro loju ona, sinu igbo, o si fi aso bo o. Nje inu OLUWA yoo dun bi mo ba mu egbeegberun aguntan wa, pelu egbegbaarun-un garawa ororo olifi? Se ki n fi akobi mi se etutu fun ese mi, ani ki n fi omo ti mo bi rubo fun ese mi? Leyin naa ni alufaa yoo fi awon ebo naa niwaju OLUWA. Mimo ni won je fun alufaa naa, pelu aya ti a fi ati itan ti won fi rubo. Leyin eyi, Nasiri naa le maa mu oti waini.Sugbon e n kegan mekunnu. Sebi awon oloro nii maa fitina yin, ti won maa n fa yin lo si kootu! OLUWA, yoo ti pe to?Ani, yoo ti pe to ti awon eniyan buruku yoo maa se jaginni?Nigba ti Jakobu n ku lo, nipa igbagbo ni o fi sure fun okookan ninu awon omo Josefu. O n sin Olorun bi o ti teriba lori opa re. Ki lo de ti eniyan buruku fi wa laaye,ti o di arugbo, ti o si di alagbara?Sugbon e n leri, e n fonnu; iru ileri bayii ko dara.Usaya tun ko awon ile iso ni Jerusalemu nibi Enubode ti o wa ni igun odi, ati si ibi Enubode afonifoji, ati nibi Isepo Odi. O si mo odi si won. E n beere pe, “Ki lo de ti ko fi gba a?” Idi re ni pe, OLUWA ni elerii majemu ti e da pelu aya ti e fe nigba ewe yin, ti e si se aisooto si, bi o tile je pe oluranlowo yin ni, oun si ni aya ti e ba da majemu. N oo si fi ajakale arun ati iku ogun se idajo won. N oo ro ojo yinyin, ina, ati imi ojo le oun, ati awon omo ogun re, ati opolopo eniyan pupo ti won wa pelu re lori. 4. Ayafi awon to gbagbo lododo
ti wọn sì n ṣe iṣẹ rere, bakan náà
ti won si n se ise rere, bakan naa
ti wọn n gba ara wọn níyànjú
ti won n gba ara won niyanju
òdodo sísọ, tí wọn sì n gba ara
ododo siso, ti won si n gba ara
wọn níyànjú ìfaradà.
won niyanju ifarada.
1. Ní Orúkọ Allah, Olôore òfẹ̀,
1. Ni Oruko Allah, Oloore ofe,
Alaáàánú jùlọ.
Alaaaanu julo.
2. Egbé ni fún olúkúlùkù abanije,
2. Egbe ni fun olukuluku abanije,
asòrọ-ẹni-lẹhìn
asoro-eni-lehin
3. Ẹni tí ô n kò ọròọ jọ, tò sì n kà á
3. Eni ti o n ko oroo jo, to si n ka a
ní àkàtúnkà.
ni akatunka.
4. Òun rò pé ọrẹ òun ni yòò mú
4. Oun ro pe ore oun ni yoo mu
òun wà gbére,
oun wa gbere,